Saamu 35:9-10

Saamu 35:9-10 BMYO

Nígbà náà ni ọkàn mi yóò yọ̀ nínú OLúWA, àní, yóò sì máa yọ̀ nínú ìgbàlà rẹ̀. Gbogbo egungun mi yóò wí pé, “Ta ni ó dàbí ì ìwọ OLúWA? O gba tálákà lọ́wọ́ àwọn tí ó lágbára jù ú lọ, tálákà àti aláìní lọ́wọ́ ẹni tí ń fi ṣe ìkógun?”