Ohun Gbogbo Dọ̀tunÀpẹrẹ

Mo ronú nígbà kan pé tí ǹ bá féràn Olórun àtipe mo se ìpinnu tí bíbélì tó dúró gboin-on, a yóò búkún mi pèlú èyà kan tí ìgbè ayé tó dára gan, tí kò sí ohun tón bani lókàn jé tàbí àjálù tàbí àìsàn. Bí mo se ń dàgbà sí i, mo bẹ̀rẹ̀ sí ni rí i díẹ̀díẹ̀ pé titèlé Olórun kò fúnni ní ìdánilójú àkójọpọ̀ àjemonú yìí, ààbò yìí. Síbè, Mo máa ń nímòlára pé tí mo ń bá see apá mi Olórun máa se siṣẹ́ àìgbọdọ̀máṣe Tíé: kó irú ayé tí a ṣojúkòkòrò fún ní Améríkà àti dáàbò bo mi lọ́wọ́ ìrora.
Nítorí àkọsílẹ̀, mo gbàgbó pé ìgboràn mú ìbúkùn àti jade pé inú Olórun dùn sí fifún wa ní nǹkan tara àti àwon èbùn,sábà máa ń jé ìdáhùn sí ti tèlé E. Kódà síbè, òye mi nípa ìjìyà se wà níbàámu—tàbí kò sí níbàámu —pèlú ìbọ́gbọ́nmu tí ìgbàgbó Kristeni tó tún tóbi jé àìkúnjú ìwọ̀n. Bíbélì jé ká mò pé ìjìyà ní àyè tirè nínú ayé wa, kódà Hébérù 2:10 sàlàyé pé a so Jésù di pípé nípasè ìjìyà. Ohun tí ñ bá tí pàdánù ní sisé yíyánhànhàn fún ohun tó mú kára tu mi àti gbigbìyànjú láti dáàbò bo àra mi látówó ohunkóhun tí mo bèrù"dé bá mi" ( ní àwon òrò Jóòbù) jé ohun tó rorun gidi gan-an: ìjìyà jé àra ìbùkún.
Kò yé kí èrò ìjìyà na owó bóòtù tí ìpayà sí àwon òkàn wa nítórí Olôrun is wà nísinsìnyí pàápàá nínú ìjìyà wa. Àmó kí a má forí le ayé ìrora, ajẹ́rìíkú, àti victimhood ní orúko’ Jésù. Kókó pàtàkì ibè, kò yé kí a bèrù ìjìyà, àmó a kò ní láti máa wáa lábé àpáta fún yálà.
Póòlù máa bẹ̀rẹ̀ létà rè sí àwọn ará Kọ́ríńtì nípa ìmorírì méjì nínú àmì ànímọ́ tí Olórun bá wa nínú àwon isé wa ìsé wa (wàhálà tàbí ìpónjú). Kíyè sí Póòlù kò so pé Olórun jé Bàbá tó láàánú, bí o tilè jé pé O jé bé, dípò Ó jé Bàbá àánú. Òun ní orísun to ìpìlesè very source and gbogbo ìyọ́nú. Òun ní àkókó àti òkan soso oní ìsun ìyọ́nú compassion’s first and only fountain—Bàbá tí gbogbo ìyọ́nú ń ṣàn láti òdò Rè. Èyí ní ìbọ́gbọ́nmu fún ènì tó rí Olórun bí ènìkan tó ń kòsí sínú ẹ̀gbẹ́ inú rere Rè lẹ́ẹ̀kọ̀ọ̀kan.
E jé ká gbé ìpìlè èdé sàyèwò ojúlówó the original èdè of the ó̩ró̩gbólóhùn àánú (ìyọ̀ọ́nú). O túmò sí “Ìfun tí èyí tí ìyọ̀ọ́nú gbé, okàn ìyọ̀ọ́nú, èrò ìmòlára àti nípa, yánhànhàn ìfárahàn àánú” tàbí “àwon ìhà inú parts.” Nígbà tí a bá wó we look at the ìtumó of this ó̩ró̩gbólóhùn, a ní òye ìmọ̀lára tó lágbára.Ní ìbámu pẹ̀lú Ìwé Mímó, mo fé jé kí o gbó lónìí pé Olúwa ní ìmọ̀lára fún o. O nífẹ̀ẹ́ è tàánútàánú àti oníyọ̀ọ́nú.
Ìwé mímọ́
Nípa Ìpèsè yìí

Ní ìrìn ajó lo sí Ìwé Kọ́ríńtì, Gbogbo ohun jé tuntun sàyèwò ẹ̀kọ́ ìsìn Póòlù tí ìgbàgbọ́ onígboyà ní ayé yìí tí Olórun pé wa láti nígboyà. Kelly Minter ràn wá lọ́wọ́ láti lóye pé ìrìn Kristeni dá bíi pé o yàtò sí ìtèsí àdánidá, àmó fí hàn dájú pé o dára jú ayérayé àti àìlópin. Ní ètò kíkà olójó márùn-ún, yóò sàyèwò àwon awuyewuye bí: bí won se yanjù àwon ìbasépò tó sòro, gbigbéklè Olórun, pèlú orúko rere rè, mimú ìdúró ìdánimọ̀ rè nínú Kristi, lilóye ète ìjìyà àti ìpèsè Olórun nínú è, àti báwo ní a se lè jé ìmọ́lẹ̀ ìhìnrere nínú ayé.
More