Ohun Èlò Bíbélì jẹ ọfẹ pátápátá, laisi ìpolówó àti àwọn rírà ni-app. Gba ohun èlò
Ààyè Ìsinmi

Ọjọ́ 5
Ǹjẹ́ ó máa ń rí lára ni ìgbàkígbà wipé ó kò gbádùn ohunkóhun nítorí ó ñ gbìyànjú láti se gbogbo ohun? Ó nse opọ̀ nǹkan lẹ́ẹ̀kan nipase ònà rè ni ayé pèlú àwon ololufe rè. . .Ó jafafa. Sùgbọ́n ó n sàárẹ̀. Ó kan ní-lò àyè èémi die. Pèlú ipèwá sókí onìyàlénu kan, Olórun pèsè ònà láti ropo ìyára rè to dùn kọjá ààlà fun èyí to ma mu àlàáfíà wa ni ìkẹyìn. Ètò yìí ma fi báwo hàn é.
A fẹ́ dúpẹ́ lọ́wọ́ North Point Ministries àti Sandra Stanley fun ìpèsè ètò yìí. Fún àlàyé síwájú síi, jọ̀wọ́ ṣe àbẹ̀wò sí: http://breathingroom.org
Àwọn Ètò tó Jẹmọ́ọ

Rin Ìrìn-Àjò Rẹ Láì Sí Ẹrú Wúwo

Àwọn Irúgbìn: Kíni àti Ìdí

Gbígbé nínú Jésù - Ètò-ẹ̀kọ́ Ìfọkànsìn Ọlọ́jọ́ Mẹ́rin lórí Ìwásáyé Jésù

Kórè Ìdúpẹ́ Yí Ọdún Ká!

Irin Ń Lọ Irin: Ẹ̀mí-sí-Ẹ̀mí® Ìtọ́ni nínú Májẹ̀mú Láéláé

Ọjọ́-Ìsinmi - Gbígbé Ìgbé-ayé ní Ìlànà Ọlọ́run

Ìrìn-àjò Hábákúùkù

Àyànfẹ́ - Níní Òye Obìnrin Nínú Krístì

Bíbélì Wà Láàyè
