1
Saamu 49:20
Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
BMYO
Ọkùnrin tí ó ní ọlá tí kò ní òye dàbí ẹranko tí ó ṣègbé.
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí Saamu 49:20
2
Saamu 49:15
Ṣùgbọ́n Ọlọ́run yóò ra ọkàn mi padà kúrò nínú isà òkú, yóò gbé mi lọ sọ́dọ̀ òun fún rara rẹ̀.
Ṣàwárí Saamu 49:15
3
Saamu 49:16-17
Má ṣe bẹ̀rù nígbà tí ẹnìkan bá di ọlọ́rọ̀. Nígbà tí ìyìn ilé rẹ̀ ń pọ̀ sí i. Nítorí kì yóò mú ohun kan lọ nígbà tí ó bá kú, ògo rẹ̀ kò ní bá a sọ̀kalẹ̀ sí ipò òkú.
Ṣàwárí Saamu 49:16-17