1
Saamu 48:14
Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
BMYO
Nítorí Ọlọ́run yìí Ọlọ́run wà ní títí ayé, Òun ni yóò ṣe amọ̀nà wa títí dè òpin ayé.
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí Saamu 48:14
2
Saamu 48:1
Ẹni ńlá ní OLúWA, tí ó sì yẹ láti máa yìn ní ìlú Ọlọ́run wa, lórí òkè mímọ́ rẹ̀.
Ṣàwárí Saamu 48:1
3
Saamu 48:10
Gẹ́gẹ́ bí orúkọ rẹ Ọlọ́run, ìyìn rẹ̀ dé òpin ayé, ọwọ́ ọ̀tún rẹ kún fún òdodo.
Ṣàwárí Saamu 48:10