1
Saamu 47:1
Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
BMYO
Ẹ pàtẹ́wọ́, gbogbo ẹ̀yin ènìyàn ẹ hó sí Ọlọ́run pẹ̀lú orin ayọ̀ tó rinlẹ̀.
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí Saamu 47:1
2
Saamu 47:2
Báwo ni OLúWA Ọ̀gá-ògo ti ní ẹ̀rù tó ọba ńlá lórí gbogbo ayé.
Ṣàwárí Saamu 47:2
3
Saamu 47:7
Nítorí Ọlọ́run ni ọba gbogbo ayé, ẹ kọrin ìyìn pẹ̀lú Saamu!
Ṣàwárí Saamu 47:7