Ọkùnrin Orí Àgbélébùú Àárín: Ètò Bíbélì Ọlọ́jọ́ Méje Tí Àjínde

Ọjọ́ 7
Ó fẹ́rẹ̀ẹ́ jẹ́ pé gbogbo ènìyàn ni ó gbà pé ayé yìí ti di ìdíbàjẹ́. Àmọ́ tí ọ̀nà àbáyọ bá wà nkọ́? Ètò àjínde ọlọ́jọ́ méje yìí bẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú ìrírí àrà ọ̀tọ̀ tí olè orí àgbélébùú, ó sì ṣe àgbéyẹ̀wò ìdí tí ìdáhùn tòótọ́ kan ṣoṣo sí ìdíbàjẹ́ fi wà ní inú pípa ọkùnrin aláìsẹ̀ kan: ìyẹn Jésù, Ọmọ Ọlọ́run.
A mú ìfọkànsìn láti inú ‘Truth For Life,’ ìwé ìfọkànsìn ojoojúmọ́ tí Alistair Begg kọ, tí The Good Book Company sì tẹ̀ jáde, thegoodbook.com. Truth For Life lò ó pẹ̀lú àṣẹ. Àṣẹ-Olóhun (C) 2022, The Good Book Company. Fún àlàyé síi, jọ̀wọ́ lọ sí: https://tfl.org/365