Bíbọ̀wá: Ìrìn Àjò Sí KérésìmesìÀpẹrẹ

Advent: The Journey to Christmas

Ọjọ́ 10 nínú 25

Olórun tó n se ohun kò seé se

Ní Lúùkù 1:34, lèyín tí ángèlì sò fún Màríà pé yóò bí Jésù,ó béèrè lówó rè, “ Báwo ní èyí máa see se, nítorí wúndíá ní mi?” Màríà se ohun tá sábà máa ń see nígbà tí a kò bá rí bi ohun máa se ṣiṣẹ́ yọrí. Ó béèrè bí nñkan kan tó dá bí pé kò seé se lè seé se.

Àmó àngélì náà dá a lohùn, “ Èmí Mímó yóò wá sórí rè, àti agbára Ènì Gíga Jù Lọ má ṣíji bò ọ́; àtipe fún ìdí èyí à yóò pè Omo Mímó náà ní Omo Olórun. Àtipe kíyèsíi, kódà mọ̀lẹ́bí rè Elisabẹti tí lóyún Omokùnrin kan náà ni ojó ògbo rè; àtipe wón pè ni àgàn lówólówó báyìí tí wá ni osù kefà rè. Nítorí kò sí ohun tó má sòrò pèlú Olórun.” 

Kódà ni àkókò tó rewà bí Kérésìmesì, o lè sòrò láti rí bí Olórun ń se sisé ni àwon ipò wa tó sòrò. Lónìí, jé kí àwon isé ìyanu méjèèjì tí ìllóyún ràn è létí nípa agbára Olórun. Ronú nípa Jésù àti omo Elisabẹti, Jòhánù Onítẹ̀bọmi, àti bí àwon ìbí wón se sàyípadà ipa-ònà ìtàn. Olórun lè se ohun aláìṣeédíwọ̀n ju bí ó tí lè finú wòye lo láàárín ìsòro rè. Gbé ipò rè fún Un, àti gbékèlé pé Yóò jé olódodo. Níṣìírí lónìí: Olórun Kò lè kùnà láé!

Àdúrà: Bàbá, E dára! Mo yìn Yín fún agbára Yín—kò sí ohun tó lè dúró lòdì sí Yín! E se pé E ní ètò fún ayé mi,fún rírán Omo Yín nítorí témí àti fún fifún mi lókun láti kojú àwon ipò ìsòro. Bí mo ń ṣẹ gbékèlé òkun Yín láìse tèmí, E ràn mi lówó láti rí Kérésìmesì gégé bí àpẹẹrẹ alágbára pé kò sohun to sòrò fún Yín.!

Gbà àwòrán tónìí jáde níbí

Ìwé mímọ́

Nípa Ìpèsè yìí

Advent: The Journey to Christmas

Ìtàn Kérésìmesì jẹ́ èyí tó ní ọlá jùlọ lóòótọ́: èyí tó dá lóríi ìṣòótọ́ Ọlọ́run, agbára, ìgbàlà, àti ìfẹ́ àìṣẹ̀tàn. Jẹ́ kí a lọ lórí ìrìn àjò ọlọ́jọ́ mẹ́ẹ̀dọ́ńgbọ̀n láti ṣe àwárí ètò pípé Ọlọ́run láti gba ayé lọ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ àti àwọn ìlérí tí a mú wá sí ìmúṣẹ nípa ìbí Ọmọ Rẹ̀.

More

A fé láti dúpe lówó Church of the Highlands fún ìpèsè ètò yìí. Fún ìsọfúnni síwájú sí i,E jòó ṣèbẹ̀wò:https://www.churchofthehighlands.com/