NIGBATI Abramu si di ẹni ọkandilọgọrun ọdún, OLUWA farahàn Abramu, o si wi fun u pe, Emi li Ọlọrun Olodumare; mã rìn niwaju mi, ki iwọ ki o si pé. Emi o si ba ọ dá majẹmu mi, emi o si sọ ọ di pupọ̀ gidigidi. Abramu si dojubolẹ; Ọlọrun si ba a sọ̀rọ pe, Bi o ṣe ti emi ni, kiyesi i, majẹmu mi wà pẹlu rẹ, iwọ o si ṣe baba orilẹ-ède pupọ̀.
Kà Gẹn 17
Feti si Gẹn 17
Pín
Fi gbogbo Èyá wéra: Gẹn 17:1-4
Ṣe àfipamọ́ àwọn ẹsẹ, kàá ní aìsìní orí ayélujára, wo àwọn àgékúrú ìkọ́ni, àti díẹ̀ síi!
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò