1
Mika 1:3
Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
YCB
Wò ó! OLúWA ń bọ̀ wá láti ibùgbé rẹ̀; yóò sọ̀kalẹ̀, yóò sì tẹ ibi gíga ayé mọ́lẹ̀.
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí Mika 1:3
2
Mika 1:1
Ọ̀rọ̀ OLúWA tí ó tọ Mika ará Moreṣeti wá ní àkókò ìjọba Jotamu, Ahasi, àti Hesekiah, àwọn ọba Juda nìwọ̀nyí, ìran tí ó rí nípa Samaria àti Jerusalẹmu.
Ṣàwárí Mika 1:1
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò