1
2 Samuẹli 23:3-4
Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
BMYO
Ọlọ́run Israẹli ni, àpáta Israẹli sọ fún mi pé, ‘Ẹnìkan ti ń ṣe alákòóso ènìyàn lódodo, tí ń ṣàkóso ní ìbẹ̀rù Ọlọ́run. Yóò sì dàbí ìmọ́lẹ̀ òwúrọ̀ nígbà tí oòrùn bá là, òwúrọ̀ tí kò ní ìkùùkuu, nígbà tí koríko tútù bá hù wá láti ilẹ̀ lẹ́yìn òjò.’
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí 2 Samuẹli 23:3-4
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò