1
AMOSI 8:11
Yoruba Bible
YCE
OLUWA Ọlọrun ní, “Ọjọ́ ń bọ̀ tí n óo rán ìyàn sí ilẹ̀ náà; kì í ṣe ìyàn, oúnjẹ, tabi ti omi, ìran láti ọ̀dọ̀ OLUWA ni kò ní sí.
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí AMOSI 8:11
2
AMOSI 8:12
Wọn yóo máa lọ káàkiri láti òkun dé òkun, láti ìhà àríwá sí ìhà ìlà oòrùn. Wọn yóo máa sá sókè sódò láti wá ọ̀rọ̀ Ọlọrun, ṣugbọn wọn kò ní rí i.
Ṣàwárí AMOSI 8:12
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò