1
Johanu 18:36
Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
BMYO
Jesu dáhùn wí pé, “Ìjọba mi kì í ṣe ti ayé yìí. Ìbá ṣe pé ìjọba mi jẹ́ ti ayé yìí, àwọn ìránṣẹ́ mi ìbá jà, kí a má ba à fi mí lé àwọn Júù lọ́wọ́, ṣùgbọ́n nísinsin yìí ìjọba mi kì í ṣe láti ìhín lọ.”
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí Johanu 18:36
2
Johanu 18:11
Nítorí náà Jesu wí fún Peteru pé, “Tẹ idà rẹ bọ inú àkọ̀ rẹ, ago tí baba ti fi fún mi, èmi ó ṣe aláìmu ún bí?”
Ṣàwárí Johanu 18:11
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò