1
Gẹnẹsisi 10:8
Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
Kuṣi sì bí Nimrodu, ẹni tí ó di alágbára jagunjagun ní ayé.
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí Gẹnẹsisi 10:8
2
Gẹnẹsisi 10:9
Ó sì jẹ́ ògbójú ọdẹ níwájú OLúWA; nítorí náà ni a ṣe ń wí pé, “Bí Nimrodu, ògbójú ọdẹ níwájú OLúWA.”
Ṣàwárí Gẹnẹsisi 10:9
YouVersion nlo awọn kuki lati ṣe adani iriri rẹ. Nipa lilo oju opo wẹẹbu wa, o gba lilo awọn kuki wa gẹgẹbi a ti ṣalaye ninu Eto Afihan wa
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò