1
2 Ọba 13:21
Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
BMYO
Bí àwọn ọmọ Israẹli kan ti ń sin òkú ọkùnrin kan, lójijì wọ́n rí ẹgbẹ́ àwọn oníjadì, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ju òkú ọkùnrin náà sínú ibojì Eliṣa. Nígbà tí ara ọkùnrin náà kan egungun Eliṣa, ó padà wá sí ayé, ó sì dúró ní ẹsẹ̀ rẹ̀.
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí 2 Ọba 13:21
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò