1
ORIN DAFIDI 53:1
Yoruba Bible
YCE
Òmùgọ̀ sọ lọ́kàn ara rẹ̀ pé, “Kò sí Ọlọrun.” Wọ́n bàjẹ́, ohun ìríra ni wọ́n ń ṣe, kò sì sí ẹnìkan ninu wọn tí ń ṣe rere.
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí ORIN DAFIDI 53:1
2
ORIN DAFIDI 53:2
Ọlọrun bojú wo àwọn ọmọ eniyan láti ọ̀run wá, ó ń wò ó bí àwọn kan bá wà tí òye yé, àní, bí àwọn kan bá wà tí ń wá Ọlọrun.
Ṣàwárí ORIN DAFIDI 53:2
3
ORIN DAFIDI 53:3
Gbogbo wọn ni ó ti yapa; tí wọn sì ti bàjẹ́, kò sí ẹnìkan tí ń ṣe rere, kò sí, bó tilẹ̀ jẹ́ ẹnìkan ṣoṣo.
Ṣàwárí ORIN DAFIDI 53:3