Àwọn ètò kíkà ọ̀fé àti àyọkà tó ní ṣe pẹ̀lú Isa 41:10

Dìde sí Ẹ̀rù Rẹ
Ojo meta
Tí a kò bá dojú kọ àwọn ohùn àìbalẹ̀àyà, iyèméjì, àtiẹ̀rù, wọn á gbàkó so ayé rẹ. O kò leè pa àwọn ohùn yìí lẹ́nu mọ tàbí kí o dá'gunlá sí wọn. Nínú ètò ẹ̀kọ́ kíkà ọlọ́jọ́ mẹ́ta yìí, Sarah Jakes Roberts fi hàn bí a ṣe lè pè níjà àwọn àsémọ́ àtẹ̀yìnwá àti bí a ṣe ń kó mọ́ra àwọn ohun tí kò rọrùn kí á lè di ẹnití kò ṣeé dá duro.

Ìdánilójú ní Àwọn Àkókò Tí Kò Sí Ìdánilójú
Ọjọ marun
Nínú àìnídánilójú, Ọlọ́run dájú! Darapọ̀ mọ́ David Villa nínú ètò ẹ̀kọ́ tuntun yìí. Ó wò kọjá àwọn àìdájú àtẹ̀yìnwá àti àìda kí ó bàa lè mú òun tó dára jù lọ.

Ṣíṣe Àwàrí Òtítọ́ Ọlọ́run Nínú Ìjì Ayé
Ọjọ́ 10
Gẹ́gẹ́ bí Kristẹni, a kò bọ́ lọ́wọ́ wàhálà nínú ayé yìí. Ìwé Jòhánù 16:33 ṣe ìlérí wípé wọn yíó wà. Tí o bá ń dojúkọ àwọn ìjì ayé ní báyìí, ètò-ìfọkànsìn yìí wà fún ọ. Ó jẹ́ ìránnilétí ìrètí tí ń mú wa la ìjì líle nínú ìgbésí ayé já. Àti pé tí o kò bá dojúkọ àwọn ìjì kankan ní àkókò yìi, yíó fún ọ ní ìpìlẹ̀ tí yíò ṣe ìrànlọ́wọ́ fún ọ láti la àwọn ìdánwò ọjọ́ iwájú kọjá.