1
Mika 6:8
Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
BMYO
Ó ti fihàn ọ́, ìwọ ènìyàn, ohun tí ó dára, àti ohun tí OLúWA ń béèrè lọ́wọ́ rẹ? Bí kò ṣe láti ṣe òtítọ́, kí o sì fẹ́ràn àánú, àti kí o rìn ní ìrẹ̀lẹ̀ pẹ̀lú Ọlọ́run rẹ̀.
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí Mika 6:8
2
Mika 6:4
Nítorí èmi mú un yín gòkè láti ilẹ̀ Ejibiti wá, mo sì rà yín padà láti ilẹ̀ ẹrú wá. Mo rán Mose láti darí yín, bákan náà mo rán Aaroni àti Miriamu síwájú rẹ̀.
Ṣàwárí Mika 6:4
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò